Gbogbo yin e sinmi ariwo e sinmi agbaja a ma se wahala jinna nitori Yahaya Bello oooooooo. Nigbati e nso nipa Yaya Bello se oun nikan ni ? Sebi gomina ni yaya ,kini e ti fe se ti baba re si Buhari gbogbo owo Liejeria to ko mi bi ejo ta lo soro nipa re ? Ti won ko ba ti mu Buhari nko ro wipe won le mu yaya bello nitoripe omo Buhari ni . E jeki won je eleyi ti won ba le je paapa julo mo fe ki won fo egungun Nigeria ki won yo mudunmudun re je . Gbogbo awon eniyan ni Liejeria lo ma je breakfast oju won ma bo . Sugbon mo mo daju pe egberun Samuel ko le sa mo Olorun lowo .
Hmmmm my father land my country o gbe enu tan
Yaya bello di abere
Mama Alaroye you are too much
Awon to nse iwode worowo ni won ma ma le kiri ati Omoyele Sowore, awon Oloselu Ole akotileta arungun.
Hmmmmm Nigeria
Please give mama O so ju mi ko ro 👍.
Ole ni gbogbo won jor!
Hello gbogbo awon ti endaruko to je agbofinro niwon ti gba riba
Oloribuku ni gbogbo won. Siooor😅
Mama Alawiye truth said God bless you ma this so calling Governors know what they doing
Kii wan mo se loo .
Olohun nbo Olohun kii se o eni ko kan oba gbogbo wan ni
Lagbara .
Olohun ju eda lo
Mama alaroye I’m sorry you didn’t tell us your name but you have a beautiful voice, ę ku isę o
Won KO ni itiju
Nigeria police don turn to Facebook bloggers police, awon ika, ole jatijati.
Gbogbo yin e sinmi ariwo e sinmi agbaja a ma se wahala jinna nitori Yahaya Bello oooooooo.
Nigbati e nso nipa Yaya Bello se oun nikan ni ? Sebi gomina ni yaya ,kini e ti fe se ti baba re si Buhari gbogbo owo Liejeria to ko mi bi ejo ta lo soro nipa re ?
Ti won ko ba ti mu Buhari nko ro wipe won le mu yaya bello nitoripe omo Buhari ni .
E jeki won je eleyi ti won ba le je paapa julo mo fe ki won fo egungun Nigeria ki won yo mudunmudun re je .
Gbogbo awon eniyan ni Liejeria lo ma je breakfast oju won ma bo .
Sugbon mo mo daju pe egberun Samuel ko le sa mo Olorun lowo .
Yahaya Bello ti di imi Eegun. A ti Peru eyi ni lu to loba to si ni ijoye.
EFCC are body of police, they are the same thing, they know where he's.
IYA ALAROYE E KU OHUN EYI LO FOJU HAN PE OLORUN NIKAN LO LE BA WA TO NIGERIA A SESE FUN WA LOLA OLORUN
God will punish y’all
Aamen